|
|
|
|
|
|
|
|
|
|
Search
|
|
Efesu 6:12 |
Nítorí pé kì í ṣe ẹ̀jẹ̀ àti ẹran ara ní awá ń bá jìjàkadì, ṣùgbọ́n àwọn ìjòyé, àwọn ọlọ́lá, àwọn aláṣẹ ìbí òkùnkùn ayé yìí, àtí àwọn ẹmí búburú ní ojú ọrun.
|
Ìfihàn 3:12 |
Ẹni tí ó ba ṣẹ́gun, òun ni èmi ó fi ṣe ọ̀wọ́n nínú tẹ́ḿpìlì Ọlọ́run mi, òun kì yóò sì jáde kúrò níbẹ̀ mọ́: èmi ó sì kọ orúkọ Ọlọ́run mi sí i lára, àti orúkọ ìlú Ọlọ́run mi, tí i ṣe Jerúsálémù tuntun, tí ó ń ti ọrun sọ̀kalẹ̀ láti ọ̀dọ̀ Ọlọ́run mi wá: àti orúkọ tuntun ti èmi tikarámì.
|
Yoruba Bible (BMY) 2014 |
Biblica Yoruba Bible |
|